1 “Kọrin, ìwọ obìnrin àgàn,
2 Fẹ ibi àgọ́ rẹ lójú sí i,
3 Nítorí ìwọ ó fẹ̀ sọ́tùn àti sí òsì;
4 “Má ṣe bẹ̀rù, ìtìjú kò ní ṣubú lù ọ́.
5 Nítorí Ẹlẹ́dàá rẹ ni ọkọ rẹ
6 Olúwa yóò pè ọ́ padà
7 “Fún ìgbà díẹ̀ ni mo kọ̀ ọ́ sílẹ̀,
8 Ní ríru ìbínú.
9 “Sí mi, èyí dàbí i àwọn ọjọ́ Noa,
10 Bí a tilẹ̀ mi àwọn òkè ńlá
11 Ìwọ ìlú tí a pọ́n lójú, tí ìjì ń gbá kiri
12 Èmi yóò fi iyùn ṣe odi rẹ,
13 Gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ ni Olúwa yóò kọ́,
14 Ní òdodo ni a ó fi ìdí rẹ kalẹ̀
15 Bí ẹnikẹ́ni bá tilẹ̀ bá ọ jà, kò ní jẹ́ láti ọwọ́ mi;
16 “Kíyèsi i, èmi ni ó dá alágbẹ̀dẹ
17 kò sí ohun ìjà tí a ṣe sí ọ tí yóò lè ṣe nǹkan,