1 Jí, jí, ìwọ Sioni,
2 Gbọn eruku rẹ kúrò;
3 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí,
4 Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí.
5 “Àti ní àkókò yìí, kí ni mo ní níbí?” ni Olúwa wí.
6 Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò mọ orúkọ mi;
7 Báwo ni ó ṣe dára tó lórí òkè
8 Tẹ́tí sílẹ̀! Àwọn olùṣọ́ rẹ gbé ohùn wọn sókè
9 Ẹ bú sí orin ayọ̀ papọ̀,
10 Olúwa yóò ṣí apá mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀
11 Ẹ túká, ẹ túká, ẹ jáde kúrò níhìn-ín yìí!
12 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kì yóò yára kúrò
13 Kíyèsi i, ìránṣẹ́ mi yóò hùwà ọlọ́gbọ́n;
14 Gẹ́gẹ́ bí a ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ tí wọ́n ń bu ọlá fún un—
15 Bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣe bomirin àwọn orílẹ̀-èdè ká,