1 “Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin tí ó ń lépa òdodo
2 ẹ wo Abrahamu baba yín,
3 Dájúdájú, Olúwa yóò tu Sioni nínú
4 “Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin ènìyàn mi;
5 Òdodo mi ń bọ̀ wá kíkankíkan,
6 Gbé ojú rẹ sókè sí àwọn ọ̀run,
7 “Ẹ gbọ́ mi, ẹ̀yin tí ó mọ ohun òtítọ́,
8 Nítorí kòkòrò yóò mú wọn lá bí aṣọ,
9 Dìde, dìde! Kí o sì wọ ara rẹ ní agbára
10 Ìwọ kọ́ ni ó gbẹ omi Òkun bí
11 Àwọn ẹni ìràpadà Olúwa yóò padà wá.
12 “Èmi, àní Èmi, èmi ni ẹni tí ó tù ọ́ nínú.
13 tí ìwọ sì gbàgbé Olúwa ẹlẹ́dàá rẹ,
14 Àwọn ẹlẹ́wọ̀n tí ń ṣojo la ó dá sílẹ̀ ní àìpẹ́ jọjọ
15 Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,
16 Mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí ẹnu rẹ
17 Jí, jí!
18 Nínú gbogbo ọmọ tí ó bí
19 Àjálù ìlọ́po ìlọ́po yìí ti dé bá ọ—
20 Àwọn ọmọkùnrin rẹ ti dákú;
21 Nítorí náà ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí a ti ṣẹ́ níṣẹ̀ẹ́,
22 Ohun tí Olúwa Olódùmarè yín wí nìyìí,
23 Èmi yóò fi lé àwọn apọ́nilójú rẹ lọ́wọ́,