1 Ohun tí Olúwa wí nìyìí:
2 Nígbà tí mo wá, èéṣe tí a kò fi rí ẹnìkan?
3 Èmi fi òkùnkùn bo sánmọ̀
4 Olúwa Olódùmarè ti fún mi ni ahọ́n tí a fi iṣẹ́ rán,
5 Olúwa Olódùmarè ti ṣí mi ní etí,
6 Mo ṣí ẹ̀yìn mi sílẹ̀ fún àwọn tí ó ń nà mí,
7 Nítorí Olúwa Olódùmarè ràn mí lọ́wọ́,
8 Ẹni tí ó dá mi láre wà nítòsí.
9 Olúwa Olódùmarè ni ó ń ràn mí lọ́wọ́.
10 Ta ni nínú yín tí ó bẹ̀rù Olúwa
11 Ṣùgbọ́n ní àkókò yìí, gbogbo ẹ̀yin ti ń tanná