1 Beli tẹrí i rẹ̀ ba, Nebo bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀;
2 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ wọ́n sì foríbalẹ̀ papọ̀;
3 “Tẹ́tí sí mi, ìwọ ilé Jakọbu,
4 Pẹ̀lúpẹ̀lú sí àwọn arúgbó àti ewú orí yín,
5 “Ta ni ìwọ yóò fi mí wé tàbí ta ni èmi yóò bá dọ́gba?
6 Ọ̀pọ̀ da wúrà sílẹ̀ nínú àpò wọn
7 Wọ́n gbé e lé èjìká wọn, wọ́n rù wọ́n,
8 “Rántí èyí, fi í sí ọkàn rẹ,
9 Rántí àwọn nǹkan àtẹ̀yìnwá, àwọn ti àtijọ́-tijọ́;
10 Mo fi òpin hàn láti ìbẹ̀rẹ̀ wá,
11 Láti ìlà-oòrùn wá ni mo ti pe ẹyẹ ajẹran wá;
12 Gbọ́ tèmi, ẹ̀yin alágídí ọkàn,
13 Èmi ń mú òdodo mi bọ̀ nítòsí,