1 “Ṣùgbọ́n gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,
2 Ohun tí Olúwa wí nìyìí
3 Nítorí èmi yóò da omi sí ilẹ̀ tí ń pòǹgbẹ
4 Wọn yóò dàgbàsókè gẹ́gẹ́ bí i koríko nínú pápá oko tútù,
5 Ọ̀kan yóò wí pé, ‘Èmi jẹ́ ti Olúwa’;
6 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí
7 Ta ni ó dàbí ì mi? Jẹ́ kí o kéde rẹ̀.
8 Má ṣe wárìrì, má ṣe bẹ̀rù.
9 Gbogbo àwọn tí ń gbẹ́ ère jásí asán,
10 Ta ni ó mọ òrìṣà kan tí ó sì ya ère,
11 Òun àti nǹkan rẹ̀ wọ̀nyí ni a ó dójútì;
12 Alágbẹ̀dẹ mú ohun èlò,
13 Gbẹ́nàgbẹ́nà fi ìwọ̀n wọ́n ọ́n
14 Ó gé igi kedari lulẹ̀,
15 Ohun èlò ìdáná ni fún ènìyàn;
16 Ìlàjì igi náà ni ó jó nínú iná;
17 Nínú èyí tí ó kù ni ó ti ṣe òrìṣà, ère rẹ̀;
18 Wọn kò mọ nǹkan kan, nǹkan kan kò yé wọn;
19 Kò sí ẹni tí ó dúró láti ronú,
20 Ó ń jẹ eérú, ọkàn ẹlẹ́tàn ni ó ṣì í lọ́nà;
21 “Rántí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ìwọ Jakọbu,
22 Èmi ti gbá gbogbo ìkùnà rẹ dànù bí i kurukuru,
23 Kọrin fáyọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, nítorí Olúwa ló ti ṣe èyí;
24 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí
25 ta ni ó ba àmì àwọn wòlíì èké jẹ́
26 ẹni tí ó gbé ọ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ jáde
27 ta ni ó sọ fún omi jíjìn pé, ‘Ìwọ gbẹ,
28 ta ni ó sọ nípa Kirusi pé, ‘Òun ni Olùṣọ́-àgùntàn mi