Isaías 44

YOR

1 “Ṣùgbọ́n gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

2 Ohun tí Olúwa wí nìyìí

3 Nítorí èmi yóò da omi sí ilẹ̀ tí ń pòǹgbẹ

4 Wọn yóò dàgbàsókè gẹ́gẹ́ bí i koríko nínú pápá oko tútù,

5 Ọ̀kan yóò wí pé, ‘Èmi jẹ́ ti Olúwa’;

6 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí

7 Ta ni ó dàbí ì mi? Jẹ́ kí o kéde rẹ̀.

8 Má ṣe wárìrì, má ṣe bẹ̀rù.

9 Gbogbo àwọn tí ń gbẹ́ ère jásí asán,

10 Ta ni ó mọ òrìṣà kan tí ó sì ya ère,

11 Òun àti nǹkan rẹ̀ wọ̀nyí ni a ó dójútì;

12 Alágbẹ̀dẹ mú ohun èlò,

13 Gbẹ́nàgbẹ́nà fi ìwọ̀n wọ́n ọ́n

14 Ó gé igi kedari lulẹ̀,

15 Ohun èlò ìdáná ni fún ènìyàn;

16 Ìlàjì igi náà ni ó jó nínú iná;

17 Nínú èyí tí ó kù ni ó ti ṣe òrìṣà, ère rẹ̀;

18 Wọn kò mọ nǹkan kan, nǹkan kan kò yé wọn;

19 Kò sí ẹni tí ó dúró láti ronú,

20 Ó ń jẹ eérú, ọkàn ẹlẹ́tàn ni ó ṣì í lọ́nà;

21 “Rántí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ìwọ Jakọbu,

22 Èmi ti gbá gbogbo ìkùnà rẹ dànù bí i kurukuru,

23 Kọrin fáyọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, nítorí Olúwa ló ti ṣe èyí;

24 “Ohun tí Olúwa wí nìyìí

25 ta ni ó ba àmì àwọn wòlíì èké jẹ́

26 ẹni tí ó gbé ọ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ jáde

27 ta ni ó sọ fún omi jíjìn pé, ‘Ìwọ gbẹ,

28 ta ni ó sọ nípa Kirusi pé, ‘Òun ni Olùṣọ́-àgùntàn mi

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado