Isaías 42

YOR

1 “Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni tí mo gbéró,

2 Òun kì yóò pariwo tàbí kígbe sókè,

3 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun kì yóò fọ́,

4 òun kì yóò kọsẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò ní rẹ̀wẹ̀sì

5 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run wí

6 “Èmi, Olúwa, ti pè ọ́ ní òdodo,

7 láti la àwọn ojú tí ó fọ́,

8 “Èmi ni Olúwa; orúkọ mi nìyìí!

9 Kíyèsi i, àwọn nǹkan àtijọ́ ti wáyé,

10 Kọ orin tuntun sí Olúwa

11 Jẹ́ kí aginjù àti àwọn ìlú rẹ̀ kí ó gbé ohùn wọn sókè;

12 Jẹ́ kí wọn fi ògo fún Olúwa

13 Olúwa yóò rìn jáde gẹ́gẹ́ bí i ọkùnrin alágbára,

14 “Fún ìgbà pípẹ́ ni mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́,

15 Èmi yóò sọ òkè ńlá àti kékeré di ahoro

16 Èmi yóò tọ àwọn afọ́jú ní ọ̀nà tí wọn kò tí ì mọ̀,

17 Ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé òrìṣà,

18 “Gbọ́, ìwọ adití,

19 Ta ló fọ́jú bí kò ṣe ìránṣẹ́ mi,

20 Ẹ̀yin ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan, ṣùgbọ́n ẹ kò ṣe àkíyèsí;

21 Ó dùn mọ́ Olúwa

22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn kan nìyìí tí a jà lógun

23 Ta ni nínú yín tí yóò tẹ́tí sí èyí

24 Ta ni ó fi Jakọbu lélẹ̀ fún ìkógun,

25 Nítorí náà ni ó ṣe rọ̀jò ìbínú un rẹ̀ lé wọn lórí,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado