1 Ègbé ni fún adé ìgbéraga,
2 Kíyèsi i, Olúwa ní ẹnìkan tí ó le, tí ó sì lágbára,
3 Adé ìgbéraga àwọn ọ̀mùtí Efraimu,
4 Òdòdó tí ó ń rọ náà tí í ṣe ẹwà ògo rẹ̀,
5 Ní ọjọ́ náà Olúwa àwọn ọmọ-ogun
6 Òun yóò sì jẹ́ ẹ̀mí ìdájọ́ òdodo
7 Àwọn wọ̀nyí pẹ̀lú ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n fún ọtí wáìnì
8 Gbogbo orí tábìlì ni ó kún fún èébì
9 “Ta ni ẹni náà tí ó ń gbìyànjú àti kọ́?
10 Nítorí tí í ṣe: báyìí ni orí,
11 Ó dára báyìí, pẹ̀lú ètè àjèjì àti ahọ́n àìmọ̀
12 àwọn tí ó sọ fún wí pé,
13 Fún ìdí èyí, ọ̀rọ̀ Olúwa sí wọn yóò di pé,
14 Nítorí náà, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ẹlẹ́gàn,
15 Ẹ fọ́n pé, “Àwa ti bá ikú mulẹ̀,
16 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
17 Èmi yóò fi ìdájọ́ ṣe okùn òsùwọ̀n
18 Májẹ̀mú yín tí ẹ bá ikú dá ni a ó fa igi lé;
19 Nígbàkígbà tí ó bá ti wá ni
20 Ibùsùn kúrú púpọ̀ fún ìnara lé lórí,
21 Olúwa yóò dìde sókè gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe
22 Ní ìsinsin yìí ẹ dákẹ́ ẹlẹ́yà ṣíṣe,
23 Tẹ́tí kí o sì gbọ́ ohùn mi,
24 Nígbà tí àgbẹ̀ kan bá tu ilẹ̀ láti gbìn
25 Nígbà tí òun bá ti tẹ́ ojú ilẹ̀ rẹ̀ pẹrẹsẹ
26 Ọlọ́run rẹ̀ tọ́ ọ ṣọ́nà
27 Nítorí a kò fi ohun èlò ìpakà dili,
28 A gbọdọ̀ lọ ìyẹ̀fun kí a tó ṣe àkàrà;
29 Gbogbo èyí pẹ̀lú ti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wá,