1 Ní ọjọ́ náà,
2 Ní ọjọ́ náà,
3 Èmi Olúwa ń bojútó o,
4 Inú kò bí mi.
5 Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, jẹ́ kí wọn wá sọ́dọ̀ mi fún ààbò;
6 Ní ọjọ́ iwájú Jakọbu yóò ta gbòǹgbò,
7 Ǹjẹ́ Olúwa ti lù ú
8 Nípa ogun jíjà àti ìjìyà ti o le ni ó
9 Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe wà
10 Ìlú olódi náà ti dahoro,
11 Nígbà tí àwọn ẹ̀ka rẹ̀ bá rọ, a ó ya wọn dànù
12 Ní ọjọ́ náà Olúwa yóò sì kó oore láti ìṣàn omi odo Eufurate wá títí dé Wadi ti Ejibiti, àti ìwọ, ìwọ ọmọ Israẹli, ni a ó kójọ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
13 Àti ní ọjọ́ náà, a ó fun fèrè ńlá kan. Gbogbo àwọn tí ń ṣègbé lọ ní Asiria àti àwọn tí ń ṣe àtìpó ní Ejibiti yóò wá sin Olúwa ní òkè mímọ́ ní Jerusalẹmu.