1 Ní ọjọ́ náà ni a ó kọ orin yìí ní ilẹ̀ Juda.
2 Ṣí àwọn ìlẹ̀kùn
3 Ìwọ yóò pa á mọ́ ní àlàáfíà pípé
4 Gbẹ́kẹ̀lé Olúwa títí láé,
5 Ó sọ àwọn tí ó ń gbé ní òkè di onírẹ̀lẹ̀
6 Ẹsẹ̀ tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀
7 Ipa ọ̀nà àwọn olódodo tẹ́jú,
8 Bẹ́ẹ̀ ni, Olúwa, rírìn ní ọ̀nà òfin rẹ
9 Ọkàn mi ń pòùngbẹẹ̀ rẹ ní ọ̀gànjọ́ òru;
10 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a fi oore-ọ̀fẹ́ hàn sí àwọn ìkà
11 Olúwa, ti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè
12 Olúwa, ìwọ fi àlàáfíà lélẹ̀ fún wa;
13 Olúwa Ọlọ́run wa, àwọn olúwa mìíràn
14 Wọ́n ti kú báyìí, wọn ò sí láààyè mọ́;
15 Ìwọ ti mú orílẹ̀-èdè gbòòrò, Olúwa;
16 Olúwa, wọ́n wá sọ́dọ̀ rẹ nínú ìpọ́njú wọn;
17 Gẹ́gẹ́ bí obìnrin tí ó lóyún tí ó sì fẹ́rẹ̀ bímọ
18 Àwa wà nínú oyún, a wà nínú ìrora,
19 Ṣùgbọ́n àwọn òkú yín yóò wà láààyè
20 Ẹ lọ, ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ wọ ìyẹ̀wù yín lọ
21 Kíyèsi i, Olúwa ń jáde bọ̀ láti ibùgbé rẹ̀