1 Èyí ni ohun tí Isaiah ọmọ Amosi rí nípa Juda àti Jerusalẹmu.
2 Ní ìgbẹ̀yìn ọjọ́
3 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò wá, wọn yóò sì wí pé,
4 Òun ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
5 Wá, ẹ̀yìn ará ilé e Jakọbu,
6 Ìwọ ti kọ àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀,
7 Ilẹ̀ wọn kún fún fàdákà àti wúrà,
8 Ilẹ̀ ẹ wọn kún fún ère,
9 Nítorí náà ni a ó ṣe rẹ ènìyàn sílẹ̀
10 Wọ inú àpáta lọ,
11 Ojú agbéraga ènìyàn ni a ó rẹ̀ sílẹ̀
12 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ọjọ́ kan ní ìpamọ́
13 nítorí gbogbo igi kedari Lebanoni, tó ga tó rìpó
14 nítorí gbogbo òkè gíga ńlá ńlá
15 fún ilé ìṣọ́ gíga gíga
16 fún gbogbo ọkọ̀ àwọn oníṣòwò
17 Ìgbéraga ènìyàn ni a ó tẹ̀ lórí ba
18 gbogbo ère òrìṣà yóò pòórá.
19 Àwọn ènìyàn yóò sálọ sínú ihò àpáta
20 Ní ọjọ́ náà ni àwọn ènìyàn yóò máa sọ
21 Wọn yóò sálọ sínú ihò ìsàlẹ̀ àpáta
22 Dẹ́kun à ń gba ènìyàn gbọ́,