Isaías 1

YOR

1 Ìran sí Juda àti Jerusalẹmu èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí ní àsìkò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah àwọn ọba Juda.

2 Gbọ́ ẹ̀yin ọ̀run! Fi etí sílẹ̀, ìwọ ayé!

3 Màlúù mọ olówó rẹ̀,

4 Á à! Orílẹ̀-èdè ẹlẹ́ṣẹ̀,

5 Èéṣe tí a ó fi tún lù yín mọ́?

6 Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín dé àtàrí yín

7 Orílẹ̀-èdè yín dahoro,

8 Ọmọbìnrin Sioni ni a fi sílẹ̀

9 Àyàfi bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun

10 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa,

11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín

12 Nígbà tí ẹ wá farahàn níwájú mi,

13 Ẹ má mú ọrẹ asán wá mọ́!

14 Ayẹyẹ oṣù tuntun yín àti àjọ̀dún tí a yàn,

15 Nígbà tí ẹ bá tẹ́ ọwọ́ yín sókè ni àdúrà,

16 “Wẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí ara yín mọ́.

17 kọ́ láti ṣe rere!

18 “Ẹ wá ní ìsinsin yìí, ẹ jẹ́ kí a jọ ṣàṣàrò,”

19 Tí ẹ̀yin bá fẹ́, tí ẹ sì gbọ́rọ̀,

20 Ṣùgbọ́n tí ẹ bá kọ̀ tí ẹ sì ṣọ̀tẹ̀,

21 Wo bí ìlú òtítọ́ ṣe di àgbèrè!

22 Fàdákà rẹ ti di ìpẹ́pẹ́,

23 Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn aláṣẹ yín,

24 Nítorí náà ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

25 Èmi yóò pa ọwọ́ mi dà sí ọ,

26 Èmi yóò mú àwọn adájọ́ rẹ bọ̀ sí ipò gẹ́gẹ́ bí i ti àtijọ́,

27 A ó fi ìdájọ́ òtítọ́ ra Sioni padà,

28 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni a ó parun.

29 “Ojú yóò tì yín nítorí igi óákù mímọ́

30 Ẹ ó sì dàbí igi óákù tí ewé rẹ̀ ti rọ,

31 Alágbára ọkùnrin náà yóò sì dàbí ohun ìdáná,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado