1 Ìran sí Juda àti Jerusalẹmu èyí tí Isaiah ọmọ Amosi rí ní àsìkò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah àwọn ọba Juda.
2 Gbọ́ ẹ̀yin ọ̀run! Fi etí sílẹ̀, ìwọ ayé!
3 Màlúù mọ olówó rẹ̀,
4 Á à! Orílẹ̀-èdè ẹlẹ́ṣẹ̀,
5 Èéṣe tí a ó fi tún lù yín mọ́?
6 Láti àtẹ́lẹsẹ̀ yín dé àtàrí yín
7 Orílẹ̀-èdè yín dahoro,
8 Ọmọbìnrin Sioni ni a fi sílẹ̀
9 Àyàfi bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun
10 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa,
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹbọ yín
12 Nígbà tí ẹ wá farahàn níwájú mi,
13 Ẹ má mú ọrẹ asán wá mọ́!
14 Ayẹyẹ oṣù tuntun yín àti àjọ̀dún tí a yàn,
15 Nígbà tí ẹ bá tẹ́ ọwọ́ yín sókè ni àdúrà,
16 “Wẹ̀ kí ẹ sì jẹ́ kí ara yín mọ́.
17 kọ́ láti ṣe rere!
18 “Ẹ wá ní ìsinsin yìí, ẹ jẹ́ kí a jọ ṣàṣàrò,”
19 Tí ẹ̀yin bá fẹ́, tí ẹ sì gbọ́rọ̀,
20 Ṣùgbọ́n tí ẹ bá kọ̀ tí ẹ sì ṣọ̀tẹ̀,
21 Wo bí ìlú òtítọ́ ṣe di àgbèrè!
22 Fàdákà rẹ ti di ìpẹ́pẹ́,
23 Ọlọ̀tẹ̀ ni àwọn aláṣẹ yín,
24 Nítorí náà ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,
25 Èmi yóò pa ọwọ́ mi dà sí ọ,
26 Èmi yóò mú àwọn adájọ́ rẹ bọ̀ sí ipò gẹ́gẹ́ bí i ti àtijọ́,
27 A ó fi ìdájọ́ òtítọ́ ra Sioni padà,
28 Ṣùgbọ́n àwọn ọlọ̀tẹ̀ àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni a ó parun.
29 “Ojú yóò tì yín nítorí igi óákù mímọ́
30 Ẹ ó sì dàbí igi óákù tí ewé rẹ̀ ti rọ,
31 Alágbára ọkùnrin náà yóò sì dàbí ohun ìdáná,