1 Ìwọ ìbá rí bí arákùnrin mi si mi,
2 Èmi ìbá fi ọ̀nà hàn ọ́
3 Ọwọ́ òsì rẹ ìbá wà ní abẹ́ orí mi,
4 Ọmọbìnrin Jerusalẹmu, èmi pè yín ní ìjà.
5 Ta ni ẹni tí ń gòkè bọ̀ wá láti aginjù,
6 Gbé mi sí àyà rẹ bí èdìdì
7 Omi púpọ̀ kò le paná ìfẹ́;
8 Àwa ní arábìnrin kékeré kan,
9 Bí òun bá jẹ́ ògiri,
10 Èmi jẹ́ ògiri,
11 Solomoni ní ọgbà àjàrà kan ní Baali-Hamoni
12 Ṣùgbọ́n ọgbà àjàrà mi jẹ́ tèmi, ó wà fún mi;
13 Ìwọ tí ń gbé inú ọgbà,
14 Yára wá, Olùfẹ́ mi,