Habacuque 2

YOR

1 Èmi yóò dúró lórí ibusọ́ mi láti máa wòye,

2 Nígbà náà ni Olúwa dáhùn pé,

3 Nítorí ìṣípayá náà jẹ́ tí ìgbà kan tí a múra sílẹ̀ dè;

4 “Kíyèsi, ọkàn rẹ tí ó gbéga,

5 Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú, nítorí tí ọtí wáìnì ni ẹ̀tàn,

6 “Gbogbo àwọn wọ̀nyí kì yóò máa pa òwe sí i tí wọn yóò sì máa kọ orin òwe sí i wí pé,

7 Ǹjẹ́ ẹni ti ó yọ ọ́ lẹ́nu, kí yóò ha dìde ní òjijì?

8 Nítorí ìwọ ti kó Orílẹ̀-èdè púpọ̀,

9 “Ègbé ni fún ẹni tí ń jẹ èrè ìjẹkújẹ sí ilé rẹ̀,

10 Ìwọ ti gbìmọ̀ ìtìjú sí ilé rẹ

11 Nítorí tí òkúta yóò kígbe jáde láti inú ògiri wá,

12 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ẹ̀jẹ̀ kọ́ ìlú,

13 Olúwa àwọn ọmọ-ogun kò ha ti ṣètò rẹ̀ pé

14 Nítorí tí ayé yóò kún fún ìmọ̀ ògo Olúwa,

15 “Ègbé ni fún ẹni tí ó fi ohun mímu fún aládùúgbò rẹ̀,

16 Ìtìjú yóò bò ọ́ dípò ògo, ìwọ náà mu pẹ̀lú

17 Nítorí ìwà ipá tí ó tí hù sí Lebanoni yóò bò ọ́,

18 “Èrè kí ni òrìṣà ni, tí oníṣọ̀nà rẹ̀ fi gbẹ́ ẹ,

19 Ègbé ni fún ẹni ti ń sọ fún igi pé, ‘Di alààyè?’

20 Ṣùgbọ́n Olúwa wà nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado