1 Fún àkàrà rẹ sórí omi,
2 Fi ìpín fún méje, àní fún mẹ́jọ pẹ̀lú,
3 Bí àwọsánmọ̀ bá kún fún omi,
4 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń wo afẹ́fẹ́ kò ní fúnrúgbìn;
5 Gẹ́gẹ́ bí ìwọ kò ti ṣe mọ ojú ọ̀nà afẹ́fẹ́
6 Fún irúgbìn rẹ ní òwúrọ̀ kùtùkùtù,
7 Ìmọ́lẹ̀ dùn;
8 Ṣùgbọ́n jẹ́ kí ènìyàn jẹ̀gbádùn gbogbo iye ọdún
9 Jẹ́ kí inú rẹ dùn, ìwọ ọ̀dọ́mọdé ní ìgbà tí o wà ní èwe
10 Nítorí náà, mú ìjayà kúrò ní ọkàn rẹ