1 Rántí Ẹlẹ́dàá rẹ
2 kí oòrùn àti ìmọ́lẹ̀
3 nígbà tí olùṣọ́ ilé yóò wárìrì
4 nígbà tí ìlẹ̀kùn sí ìgboro yóò tì
5 Nígbà tí ènìyàn yóò bẹ̀rù ibi gíga
6 Rántí rẹ̀ kí okùn fàdákà tó já,
7 Tí erùpẹ̀ yóò sì padà sí ilẹ̀ ibi tí ó ti wà,
8 “Asán! Asán!” ni Oniwaasu wí.
9 Kì í ṣe wí pé Oniwaasu jẹ́ ọlọ́gbọ́n nìkan, ṣùgbọ́n ó tún kọ́ àwọn ènìyàn ní ìmọ̀. Ó rò ó dáradára ó sì ṣe àwárí, ó sì gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ òwe kalẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ.
10 Oniwaasu wádìí láti rí àwọn ọ̀rọ̀ tí ó tọ̀nà, ohun tí ó kọ sì dúró ṣinṣin ó sì jẹ́ òtítọ́.
11 Ọ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n dàbí ẹ̀gún, àkójọpọ̀ ọ̀rọ̀ wọn sì dàbí ìṣó tí a kàn pọ̀ dáradára, tí olùṣọ́-àgùntàn kan fi fún ni.
12 Àti síwájú láti inú èyí, ọmọ mi, gba ìmọ̀ràn.
13 Nísinsin yìí,
14 Nítorí Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ olúkúlùkù iṣẹ́