Amós 9

YOR

1 Mo rí Olúwa, ó dúró ní ẹ̀bá pẹpẹ, ó sì wí pé:

2 Bí wọ́n tilẹ̀ wa ilẹ̀ lọ sí ipò òkú,

3 Bí wọ́n tilẹ̀ fi ara wọn pamọ́ ni orí òkè Karmeli,

4 Bí wọ́n tilẹ̀ lọ sí ìgbèkùn ní iwájú àwọn ọ̀tá wọn

5 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

6 Òun ni ẹni tí ó kọ́ ìtẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ọ̀run

7 “Àbá ẹ̀yin ọmọ Israẹli

8 “Dájúdájú, ojú Olúwa Olódùmarè

9 “Nítorí Èmi yóò pàṣẹ,

10 Gbogbo àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn mi

11 “Ní ọjọ́ náà ní

12 kí wọn le jogún ìyókù Edomu

13 “Ọjọ́ náà ń bọ,” ni Olúwa wí,

14 Èmi yóò si tún mú ìgbèkùn Israẹli ènìyàn mi padà bọ̀.

15 Èmi yóò gbin Israẹli sí orí ilẹ̀ rẹ̀.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado