1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa ti sọ nípa rẹ̀, ẹ̀yin ènìyàn Israẹli nípa àwọn ìdílé tí mo mú jáde láti Ejibiti:
2 “Ìwọ nìkan ni ẹni tí mo yàn
3 Ẹni méjì ha à le rìn pọ̀
4 Ǹjẹ́ Kìnnìún yóò ha bú ramúramù nínú igbó,
5 Ǹjẹ́ ẹyẹ ṣubú sínú okùn ọdẹ lórí ilẹ̀
6 Nígbà tí ìpè bá dún ní ìlú,
7 Nítòótọ́ Olúwa Olódùmarè kò ṣe ohun kan
8 Kìnnìún ti bú ramúramù
9 Ẹ kéde ní ààfin Aṣdodu
10 “Wọn kò mọ bí wọ́n ṣe ń ṣe rere,” ni Olúwa wí,
11 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
12 Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
13 “Gbọ́ èyí kí o sì jẹ́rìí nípa ilé Jakọbu,” ni Olúwa wí, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun.
14 “Ní ọjọ́ tí mo fìyà jẹ Israẹli lórí ẹ̀ṣẹ̀ wọn,
15 Èmi yóò wó ilé òtútù