1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀.
2 Àti Hamati pẹ̀lú yóò ṣe ààlà rẹ̀
3 Tire sì mọ odi líle fún ara rẹ̀,
4 Ṣùgbọ́n, Olúwa yóò kó gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ,
5 Aṣkeloni yóò rí í, yóò sì bẹ̀rù;
6 Ọmọ àlè yóò sì gbé inú Aṣdodu,
7 Èmi yóò sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ kúrò ni ẹnu rẹ̀,
8 Èmi yóò sì dó yí ilẹ̀ mi ká
9 Kún fún ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni,
10 Èmi ó sì gbé kẹ̀kẹ́ kúrò ni Efraimu,
11 Ní tìrẹ, nítorí ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ,
12 Ẹ padà sínú odi agbára yín, ẹ̀yin òǹdè ti o ni ìrètí:
13 Èmi ó fa Juda le bí mo ṣe fa ọrun mi le,
14 Olúwa yóò sì fi ara hàn ní orí wọn;
15 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bò wọ́n;
16 Olúwa Ọlọ́run wọn yóò sì gbà wọ́n là ni ọjọ́ náà
17 Nítorí oore rẹ̀ tí tóbi tó, ẹwà rẹ̀ sì tí pọ̀!