1 Olúwa jẹ ọba;
2 Olúwa tóbi ní Sioni;
3 Kí wọ́n sì yin orúkọ rẹ̀ tí ó tóbi
4 Ọba náà ní agbára, ó sì fẹ́ òdodo,
5 Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa
6 Mose àti Aaroni wà nínú àwọn àlùfáà rẹ̀
7 Ó sọ̀rọ̀ sí wọn nínú ọ̀wọ́n àwọsánmọ̀,
8 Olúwa Ọlọ́run wa, ó dá wọn lóhùn;
9 Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa