Salmos 9

YOR

1 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;

2 Inú mi yóò dùn, èmi yóò sì yọ̀ nínú rẹ;

3 Àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà;

4 Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ọ̀ràn mi mú;

5 Ìwọ ti bá orílẹ̀-èdè wí, Ìwọ sì ti pa ẹni búburú run;

6 Ìparun àìlópin ti borí àwọn ọ̀tá,

7 Olúwa jẹ ọba títí láé;

8 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ ayé ní òdodo;

9 Olúwa ni ààbò fún àwọn tí a ni lára,

10 Àwọn tí ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀lé ọ,

11 Kọ orin ìyìn sí Olúwa, tí o ń jẹ ọba ní Sioni;

12 Nítorí ẹni tí ó ń gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ rántí;

13 Olúwa, wo bí àwọn ọ̀tá ṣe ń ṣe inúnibíni sí mi!

14 kí èmi kí ó lè sọ ti ìyìn rẹ

15 Àwọn orílẹ̀-èdè ti jì sí kòtò tí wọn ti gbẹ́;

16 A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀;

17 Àwọn ènìyàn búburú ni a ó dà sí isà òkú,

18 Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a kò ní gbàgbé láéláé,

19 Dìde, Olúwa, má ṣe jẹ́ kí ènìyàn borí;

20 Lù wọ́n pẹ̀lú ìpayà, Olúwa;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado