1 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi;
2 Inú mi yóò dùn, èmi yóò sì yọ̀ nínú rẹ;
3 Àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà;
4 Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ọ̀ràn mi mú;
5 Ìwọ ti bá orílẹ̀-èdè wí, Ìwọ sì ti pa ẹni búburú run;
6 Ìparun àìlópin ti borí àwọn ọ̀tá,
7 Olúwa jẹ ọba títí láé;
8 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ ayé ní òdodo;
9 Olúwa ni ààbò fún àwọn tí a ni lára,
10 Àwọn tí ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀lé ọ,
11 Kọ orin ìyìn sí Olúwa, tí o ń jẹ ọba ní Sioni;
12 Nítorí ẹni tí ó ń gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ rántí;
13 Olúwa, wo bí àwọn ọ̀tá ṣe ń ṣe inúnibíni sí mi!
14 kí èmi kí ó lè sọ ti ìyìn rẹ
15 Àwọn orílẹ̀-èdè ti jì sí kòtò tí wọn ti gbẹ́;
16 A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀;
17 Àwọn ènìyàn búburú ni a ó dà sí isà òkú,
18 Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a kò ní gbàgbé láéláé,
19 Dìde, Olúwa, má ṣe jẹ́ kí ènìyàn borí;
20 Lù wọ́n pẹ̀lú ìpayà, Olúwa;