Salmos 10

YOR

1 Èéha ti ṣe, Olúwa, tí ìwọ fi dúró ní òkè réré?

2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú tí mu aláìlera,

3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀;

4 Ènìyàn búburú kò lè rí nínú ìgbéraga rẹ̀;

5 Ọ̀nà rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo;

6 O wí fún ara rẹ̀, “Kò sí ohun tí ó lè mì mí.

7 Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ;

8 Ó lúgọ ní bùba nítòsí ìletò.

9 Ó ba ní ní bùba bí i kìnnìún nínú pàǹtí;

10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀;

11 Ó wí fún ara rẹ̀, “Ọlọ́run ti gbàgbé;

12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run.

13 Èéṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run?

14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó rí wàhálà àti ìrora;

15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi;

16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé;

17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára;

18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado