1 Èéha ti ṣe, Olúwa, tí ìwọ fi dúró ní òkè réré?
2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú tí mu aláìlera,
3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀;
4 Ènìyàn búburú kò lè rí nínú ìgbéraga rẹ̀;
5 Ọ̀nà rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo;
6 O wí fún ara rẹ̀, “Kò sí ohun tí ó lè mì mí.
7 Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ;
8 Ó lúgọ ní bùba nítòsí ìletò.
9 Ó ba ní ní bùba bí i kìnnìún nínú pàǹtí;
10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀;
11 Ó wí fún ara rẹ̀, “Ọlọ́run ti gbàgbé;
12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run.
13 Èéṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run?
14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó rí wàhálà àti ìrora;
15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi;
16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé;
17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára;
18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára,