Salmos 88

YOR

1 Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là,

2 Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ;

3 Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú

4 A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀

5 A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú

6 Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn,

7 Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi;

8 Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi

9 ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú.

10 Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi?

11 A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí,

12 A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí

13 Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa;

14 Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí

15 Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi,

16 Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi;

17 Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi;

18 Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado