Salmos 71

YOR

1 Nínú rẹ, Olúwa, ni mo ní ààbò;

2 Gbà mí kí o sì tú mi sílẹ̀ nínú òdodo rẹ;

3 Jẹ́ àpáta ààbò mi,

4 Gbà mí, Ọlọ́run mi, lọ́wọ́ àwọn olùṣe búburú,

5 Nítorí ìwọ jẹ́ ìrètí mi, Olúwa Olódùmarè,

6 Mo gbẹ́kẹ̀lé ọ láti ìgbà ìbí mi;

7 Mo di àmì fún ọ̀pọ̀ ènìyàn,

8 Ìyìn rẹ̀ kún ẹnu mi,

9 Má ṣe ta mí nù ní ọjọ́ ogbó mi,

10 Nítorí àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀-òdì sí mi,

11 Wọ́n wí pé, “Ọlọ́run ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀;

12 Má ṣe jìnnà sí mi, Ọlọ́run;

13 Jẹ́ kí wọn kí ó dààmú,

14 Ṣùgbọ́n ní tèmi, ìgbà gbogbo ní ìrètí mi;

15 Ẹnu mi yóò sọ nípa ti òdodo rẹ,

16 Èmi ó wá láti wá kéde agbára,

17 Láti ìgbà èwe, Ọlọ́run ni ìwọ ti kọ́ mi

18 Pẹ̀lúpẹ̀lú, nígbà tí èmi di arúgbó tán tí mo sì hewú,

19 Ọlọ́run, òdodo rẹ dé ọ̀run,

20 Pẹ̀lúpẹ̀lú ìwọ ti mú mi rí ìdààmú, tí ó pọ̀ tí ó sì korò,

21 Ìwọ yóò fi kún ọwọ́ mi

22 Èmi yóò fi dùùrù mi yìn

23 Ètè mi yóò kígbe fún ìyìn

24 Ahọ́n mi yóò sọ ti òdodo rẹ ní gbogbo ọjọ́,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado