Salmos 48

YOR

1 Ẹni ńlá ní Olúwa, tí ó sì yẹ láti máa yìn

2 Ó dára nínú ipò ìtẹ́ rẹ̀,

3 Ọlọ́run wà nínú ààbò ààfin rẹ̀;

4 Nígbà tí àwọn ọba kógun jọ pọ̀,

5 Wọn rí i, bẹ́ẹ̀ ni ẹnu sì yà wọ́n,

6 Ẹ̀rù sì bà wọ́n níbẹ̀,

7 Ìwọ bà wọ́n jẹ́ gẹ́gẹ́ bí ọkọ̀ orí omi Tarṣiṣi,

8 Gẹ́gẹ́ bí a ṣe gbọ́,

9 Láàrín tẹmpili rẹ, Ọlọ́run,

10 Gẹ́gẹ́ bí orúkọ rẹ Ọlọ́run,

11 Jẹ́ kí òkè Sioni kí ó yọ̀

12 Rìn Sioni kiri lọ yíká rẹ̀,

13 Kíyèsi odi rẹ̀,

14 Nítorí Ọlọ́run yìí Ọlọ́run wà ní títí ayé,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado