1 Ọlọ́run ni ààbò àti agbára wa
2 Nítorí náà àwa kì yóò bẹ̀rù, bí a tilẹ̀ ṣí ayé ní ìdí,
3 Tí omi rẹ̀ tilẹ̀ ń hó tí ó sì ń mì
4 Odò ńlá kan wà tí ṣíṣàn rẹ̀ mú inú ìlú Ọlọ́run dùn,
5 Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀, kò ní yẹ̀:
6 Àwọn orílẹ̀-èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba ṣubú,
7 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa,
8 Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwa
9 O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayé
10 Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́run.
11 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa;