Salmos 46

YOR

1 Ọlọ́run ni ààbò àti agbára wa

2 Nítorí náà àwa kì yóò bẹ̀rù, bí a tilẹ̀ ṣí ayé ní ìdí,

3 Tí omi rẹ̀ tilẹ̀ ń hó tí ó sì ń mì

4 Odò ńlá kan wà tí ṣíṣàn rẹ̀ mú inú ìlú Ọlọ́run dùn,

5 Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀, kò ní yẹ̀:

6 Àwọn orílẹ̀-èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba ṣubú,

7 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa,

8 Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwa

9 O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayé

10 Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́run.

11 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado