1 À ti fi etí wa gbọ́, Ọlọ́run;
2 Ìwọ fi ọwọ́ rẹ lé orílẹ̀-èdè jáde,
3 Kì í ṣe nípa idà wọn ni wọ́n gba ilẹ̀ náà,
4 Ìwọ ni ọba àti Ọlọ́run mi,
5 Nípasẹ̀ rẹ ni àwa ó bi àwọn ọ̀tá wa ṣubú;
6 èmi kì yóò gbẹ́kẹ̀lé ọrun mi,
7 ṣùgbọ́n ìwọ fún wa ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọ̀tá wa,
8 Nínú Ọlọ́run àwa ń ṣògo ní gbogbo ọjọ́,
9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ ti kọ̀ wá, ìwọ sì ti dójútì wá,
10 Ìwọ ti bá wa jà,
11 Ìwọ fi wá fún jíjẹ bí ẹran àgùntàn,
12 Ìwọ ta àwọn ènìyàn rẹ fún owó kékeré,
13 Ìwọ sọ wá di ẹni ẹ̀sín ní ọ̀dọ̀ àwọn aládùúgbò wa,
14 Ìwọ ti sọ wá di ẹni ìfisọ̀rọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè;
15 Ìdójútì mi ń bẹ pẹ̀lú mi ní gbogbo ọjọ́,
16 nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn àti ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn
17 Gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí ń ṣẹlẹ̀ sí wa,
18 Ọkàn wa kò padà sẹ́yìn;
19 Ṣùgbọ́n wọ́n kọlù wá,
20 Bí àwa bá ti gbàgbé orúkọ Ọlọ́run wa
21 Ǹjẹ́ Ọlọ́run kì yóò rí ìdí rẹ̀,
22 Síbẹ̀, nítorí rẹ̀ àwa da àyà kọ ikú, ní ojoojúmọ́
23 Jí, Olúwa! Èéṣe tí ìwọ ń sùn?
24 Èéṣe tí ìwọ ń pa ojú rẹ mọ́
25 Nítorí a tẹrí ọkàn wa ba sínú eruku;
26 Dìde kí o sì ràn wá lọ́wọ́;