Salmos 149

YOR

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.

2 Jẹ́ kí Israẹli kí ó ní inú dídùn sí ẹni tí ó dá a

3 Jẹ́ kí wọn kí ó fi ijó yin orúkọ rẹ̀

4 Nítorí Olúwa ní inú dídùn sí àwọn ènìyàn rẹ̀

5 Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mímọ́ kí ó yọ̀ nínú ọlá rẹ̀

6 Kí ìyìn Ọlọ́run kí ó wà ní ẹnu wọn

7 Láti gba ẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè,

8 láti fi ẹ̀wọ̀n de àwọn ọba wọn

9 Láti ṣe ìdájọ́ tí àkọsílẹ̀ rẹ̀ sí wọn

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado