Salmos 147

YOR

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.

2 Olúwa kọ́ Jerusalẹmu;

3 Ó wo àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn

4 Ó ka iye àwọn ìràwọ̀

5 Títóbi ni Olúwa wa ó sì pọ̀ ní agbára

6 Olúwa wa pẹ̀lú àwọn onírẹ̀lẹ̀

7 Fi ọpẹ́ kọrin sí Olúwa

8 Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀

9 Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko

10 Òun kò ní inú dídùn nínú agbára ẹṣin,

11 Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,

12 Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu;

13 Nítorí tí ó ti mú ọ̀pá ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára,

14 Òun jẹ́ kí àlàáfíà wà ní àwọn ẹnu ibodè rẹ̀,

15 Òun sì rán àṣẹ rẹ̀ sí ayé

16 Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn

17 Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ bí òkúta wẹ́wẹ́

18 Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó sì mú wọn yọ̀

19 Ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ di mí mọ̀ fún Jakọbu

20 Òun kó tí ṣe irú èyí sí orílẹ̀-èdè kan rí, bí ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado