Salmos 135

YOR

1 Ẹ yin Olúwa.

2 Ẹ̀yin tí ń dúró ní ilé Olúwa,

3 Ẹ yin Olúwa: nítorí tí Olúwa ṣeun;

4 Nítorí tí Olúwa ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀;

5 Nítorí tí èmi mọ̀ pé Olúwa tóbi,

6 Olúwa ṣe ohunkóhun tí ó wù ú,

7 Ó mú ìkùùkuu gòkè láti òpin ilẹ̀ wá:

8 Ẹni tí ó kọlu àwọn àkọ́bí Ejibiti,

9 Ẹni tí ó rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu sí àárín rẹ̀, ìwọ Ejibiti,

10 Ẹni tí ó kọlu àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀,

11 Sihoni, ọba àwọn ará Amori, àti Ogu,

12 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,

13 Olúwa orúkọ rẹ dúró láéláé;

14 Nítorí tí Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀,

15 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,

16 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀;

17 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀;

18 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn:

19 Ẹ̀yin ara ilé Israẹli, ẹ fi ìbùkún fún Olúwa,

20 Ẹ̀yin ará ilé Lefi, fi ìbùkún fún Olúwa;

21 Olùbùkún ni Olúwa, láti Sioni wá,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado