Salmos 122

YOR

1 Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé,

2 Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ,

3 Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú

4 Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ,

5 Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀,

6 Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu;

7 Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀,

8 Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi

9 Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado