1 Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé,
2 Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ,
3 Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú
4 Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ,
5 Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀,
6 Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu;
7 Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀,
8 Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi
9 Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa,