1 Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì—
2 Ìrànlọ́wọ́ mi tí ọwọ́ Olúwa wá,
3 Òun kì yóò jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó yẹ̀;
4 Kíyèsi, ẹni tí ń pa Israẹli mọ́,
5 Olúwa ni olùpamọ́ rẹ;
6 Oòrùn kì yóò pa ọ́ ní ìgbà ọ̀sán
7 Olúwa yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú ibi gbogbo
8 Olúwa yóò pa àlọ àti ààbọ̀ rẹ mọ́