Salmos 119

YOR

1 Ìbùkún ni fún àwọn ẹni tí ọ̀nà wọn wà láìlẹ́ṣẹ̀,

2 Ìbùkún ni fún àwọn ẹni tí ń pa òfin rẹ̀ mọ́

3 Wọn kò ṣe ohun tí kò dára;

4 Ìwọ ti la ìlànà rẹ̀ sílẹ̀

5 Ọ̀nà mi ìbá dúró ṣinṣin

6 Nígbà náà, ojú kò ní tì mí

7 Èmi yóò yìn ọ́ pẹ̀lú ọkàn ìdúró ṣinṣin

8 Èmi yóò gbọ́rọ̀ sí àṣẹ rẹ̀,

9 Báwo ni àwọn ọ̀dọ́ yóò ti ṣe pa ọ̀nà rẹ̀ mọ́?

10 Èmi wá ọ pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi

11 Èmi ti pa ọ̀rọ̀ rẹ mọ́ ní ọkàn mi

12 Ìyìn ni fún Olúwa;

13 Pẹ̀lú ètè mi èmi tún ṣírò

14 Èmi ń yọ̀ ní ọ̀nà ẹ̀rí rẹ,

15 Èmi ń ṣe àṣàrò nínú ìlànà rẹ

16 Inú mi dùn sí àṣẹ rẹ;

17 Ṣe rere sí ìránṣẹ́ rẹ, èmi yóò sì wà láààyè;

18 La ojú mi kí èmi lè ríran rí

19 Àlejò ní èmi jẹ́ láyé,

20 Ọkàn mi pòruurù pẹ̀lú ìfojúsọ́nà

21 Ìwọ fi àwọn agbéraga bú, àwọn tí a fi gégùn ún

22 Mú ẹ̀gàn àti àbùkù kúrò lára mi,

23 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn alákòóso kójọpọ̀,

24 Òfin rẹ ni dídùn inú mi;

25 Ọkàn mí lẹ̀ mọ́ erùpẹ̀;

26 Èmi tún ọ̀nà mi ṣírò ìwọ sì dá mi lóhùn;

27 Jẹ́ kí n mọ ẹ̀kọ́ ìlànà rẹ:

28 Ọkàn mi ń ṣe àárẹ̀ pẹ̀lú ìbànújẹ́;

29 Pa mí mọ́ kúrò nínú ọ̀nà ẹ̀tàn

30 Èmi ti yan ọ̀nà òtítọ́

31 Èmi yára di òfin rẹ mú. Olúwa

32 Èmi sáré ní ipa ọ̀nà àṣẹ rẹ,

33 Kọ́ mi, Olúwa, láti tẹ̀lé àṣẹ rẹ;

34 Fún mi ní òye, èmi yóò sì pa òfin rẹ mọ́

35 Fi ipa ọ̀nà àṣẹ rẹ hàn mí,

36 Yí ọkàn mi padà sí òfin rẹ

37 Yí ojú mi padà kúrò láti máa wo ohun asán:

38 Mú ìlérí rẹ sẹ sí ìránṣẹ́ rẹ,

39 Yí ẹ̀gàn mi padà tí mo bẹ̀rù

40 Kíyèsi i, ọkàn mi ti fà sí ẹ̀kọ́ rẹ!

41 Jẹ́ kí ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà wá bá mi, Olúwa,

42 Nígbà náà ni èmi yóò dá

43 Má ṣe gba ọ̀rọ̀ òtítọ́ láti ẹnu mi

44 Èmi yóò máa gbọ́rọ̀ sí òfin rẹ nígbà gbogbo

45 Èmi yóò máa rìn káàkiri ní òmìnira,

46 Èmi yóò sọ̀rọ̀ òfin rẹ níwájú àwọn ọba

47 nítorí èmi ní inú dídùn nínú àṣẹ rẹ

48 Èmi gbé ọwọ́ mi sókè nítorí àṣẹ rẹ, èyí tí èmi fẹ́ràn,

49 Rántí ọ̀rọ̀ rẹ sí ìránṣẹ́ rẹ,

50 Ìtùnú mi nínú ìpọ́njú mi ni èyí:

51 Àwọn agbéraga fi mí ṣe ẹlẹ́yà láì dádúró,

52 Èmi rántí àwọn òfin rẹ ìgbàanì, Olúwa,

53 Ìbínú dì mímú ṣinṣin nítorí àwọn ẹni búburú,

54 Òfin rẹ ni ọ̀rọ̀ ìpìlẹ̀ orin mi

55 Ní òru èmi rántí orúkọ rẹ, Olúwa,

56 nítorí tí mo

57 Ìwọ ni ìpín mi, Olúwa:

58 Èmi ti wá ojú rẹ pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi:

59 Èmi ti kíyèsi ọ̀nà mi

60 Èmi yóò yára, ń kò ni lọ́ra

61 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ẹni búburú dì mí pẹ̀lú okùn,

62 Ní àárín ọ̀gànjọ́ òru èmi dìde láti fi ọpẹ́ fún ọ

63 Èmi jẹ́ ọ̀rẹ́ sí gbogbo àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ,

64 Ayé kún fún ìfẹ́ rẹ, Olúwa,

65 Ṣe rere sí ìránṣẹ́ rẹ

66 Kọ́ mi ní ìmọ̀ àti ìdájọ́ rere,

67 Kí a tó pọ́n mi lójú èmi ti ṣìnà,

68 Ìwọ dára, ohun tí ìwọ sì ń ṣe rere ni;

69 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn agbéraga ti gbìmọ̀ èké sí mí,

70 Ọkàn wọn yigbì kò sì ní àánú,

71 Ó dára fún mi kí a pọ́n mi lójú

72 Òfin tí ó jáde láti ẹnu rẹ ju iyebíye sí mi lọ

73 Ọwọ́ rẹ ni ó dá mi tí ó sì mọ mí;

74 Jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ máa yọ̀ nígbà tí wọ́n bá rí mi,

75 Èmi mọ, Olúwa, nítorí òfin rẹ òdodo ni,

76 Kí ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà jẹ́ ìtùnú mi,

77 Jẹ́ kí àánú rẹ kí ó tọ̀ mí wá, kí èmi kí ó lè yè,

78 Kí ojú kí ó ti àwọn agbéraga

79 Kí àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ yí padà sí mi,

80 Jẹ́ kí ọkàn mi wà láìlẹ́bi sí òfin rẹ,

81 Ọkàn mi ń fojú ṣọ́nà nítorí ìgbàlà rẹ,

82 Ojú mi kùnà, pẹ̀lú wíwo ìpinnu rẹ;

83 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi dàbí awọ-wáìnì lójú èéfín,

84 Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò ṣe dúró pẹ́ tó?

85 Àwọn agbéraga wa ihò ìṣubú fún mi,

86 Gbogbo àṣẹ rẹ yẹ ní ìgbẹ́kẹ̀lé;

87 Wọ́n fẹ́rẹ pa mí rẹ́ kúrò nínú ayé,

88 Pa ayé mi mọ́ gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ,

89 Ọ̀rọ̀ rẹ, Olúwa, títí láé ni;

90 Òtítọ́ rẹ̀ ń lọ dé gbogbo ìran dé ìran;

91 Òfin rẹ dúró di òní

92 Bí òfin rẹ̀ kò bá jẹ́ dídùn inú mi,

93 Èmi kì yóò gbàgbé ẹ̀kọ́ rẹ láé,

94 Gbà mí, nítorí èmi jẹ́ tìrẹ

95 Àwọn ẹni búburú dúró láti pa mí run,

96 Sí ohun pípé gbogbo èmi ti rí òpin;

97 Báwo ni èmi ti fẹ́ òfin rẹ tó!

98 Àṣẹ rẹ mú mi gbọ́n ju àwọn ọ̀tá mi lọ,

99 Èmi ní iyè inú ju gbogbo olùkọ́ mi lọ,

100 Èmi ni òye ju àwọn àgbà lọ,

101 Èmi ti pa ẹsẹ̀ mi mọ́ nínú gbogbo ọ̀nà ibi

102 Èmi kò yà kúrò nínú òfin rẹ,

103 Báwo ni ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣe dùn mọ́ mi lẹ́nu tó,

104 Èmi rí òye gbà nínú ẹ̀kọ́ rẹ;

105 Ọ̀rọ̀ rẹ ni fìtílà sí ẹsẹ̀ mi

106 Èmi ti ṣe ìbúra èmi sì ti tẹnumọ́ ọn

107 A pọ́n mi lójú gidigidi;

108 Olúwa, gba ìyìn àtinúwá ẹnu mi,

109 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ayé mi wà ni ọwọ́ mi nígbà gbogbo,

110 Àwọn ẹni búburú ti dẹ okùn sílẹ̀ fún mi,

111 Òfin rẹ ni ogún mi láéláé;

112 Ọkàn mi ti lé pípa òfin rẹ mọ́

113 Èmi kórìíra àwọn ọlọ́kàn méjì,

114 Ìwọ ni ààbò mi àti asà mi;

115 Ẹ kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ̀yin olùṣe búburú,

116 Gbé mi sókè gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ,

117 Gbé mi sókè, èmí yóò sì wa láìléwu;

118 Ìwọ kọ gbogbo àwọn tí ó ṣìnà kúrò nínú òfin rẹ,

119 Gbogbo àwọn ẹni búburú ní ayé ni ìwọ yọ kúrò bí i ìdàrọ́;

120 Ara mi wárìrì ní ìbẹ̀rù nítorí rẹ̀:

121 Èmi ti ṣe ohun tí i ṣe òdodo àti ẹ̀tọ́:

122 Mú kí àlàáfíà ìránṣẹ́ rẹ dájú:

123 Ojú mi kùnà, fún wíwo ìgbàlà rẹ,

124 Ṣe pẹ̀lú ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí dídúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ

125 Èmi ni ìránṣẹ́ rẹ; ẹ fún mi ní òye

126 Ó tó àsìkò fún ọ láti ṣe iṣẹ́, Olúwa;

127 Nítorí èmi fẹ́ràn àṣẹ rẹ

128 nítorí èmi kíyèsi gbogbo ẹ̀kọ́ òtítọ́ rẹ̀,

129 Òfin rẹ̀ ìyanu ni:

130 Ìṣípayá ọ̀rọ̀ rẹ̀ mú ìmọ́lẹ̀ wá;

131 Èmi ya ẹnu mi mo sì mí hẹlẹ,

132 Yí padà sí mi kí o sì ṣàánú fún mi,

133 Fi ìṣísẹ̀ mi múlẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ rẹ,

134 Rà mí padà lọ́wọ́ aninilára ènìyàn,

135 Jẹ́ kí ojú rẹ kí ó tàn sí ìránṣẹ́ rẹ lára

136 Omijé sàn jáde ní ojú mi,

137 Olódodo ni ìwọ Olúwa

138 Òfin ti ìwọ gbé kalẹ̀ jẹ́ òdodo:

139 Ìtara mi ti pa mí run,

140 Wọ́n ti dán ìpinnu rẹ wò pátápátá

141 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ àti ẹni ẹ̀gàn

142 Òdodo rẹ wà títí láé

143 Ìyọnu àti ìpọ́njú wá sórí mi,

144 Òfin rẹ jẹ́ òtítọ́ láé;

145 Èmi kígbe pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi:

146 Èmi kígbe pè ọ́; gbà mí

147 Èmi dìde ṣáájú àfẹ̀mọ́júmọ́ èmi ké fún ìrànlọ́wọ́;

148 Ojú mi ṣáájú ìṣọ́ òru,

149 Gbọ́ ohùn mi ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú ìfẹ́ rẹ:

150 Àwọn tí ń gbìmọ̀ ìlànà búburú wà ní tòsí,

151 Síbẹ̀ ìwọ wà ní tòsí, Olúwa,

152 Láti ọjọ́ pípẹ́ wá èmi ti kọ́ nínú òfin rẹ

153 Wo ìpọ́njú mi kí o sì gbà mí,

154 Gba ẹjọ́ mi rò kí o sì rà mí padà;

155 Ìgbàlà jìnnà sí àwọn ẹni búburú

156 Ìyọ́nú rẹ̀ tóbi, Olúwa;

157 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn ọ̀tá tí wọ́n ń ṣe inúnibíni sí mi,

158 Èmi wo àwọn ẹlẹ́tàn, inú mi sì bàjẹ́

159 Wo bí èmi ṣe fẹ́ràn ẹ̀kọ́ rẹ;

160 Òtítọ́ ni gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ;

161 Àwọn alákòóso ṣe inúnibíni sí mi láìnídìí,

162 Èmi yọ̀ nínú ìpinnu rẹ

163 Èmi kórìíra mo sì kọ èké ṣíṣe

164 Èmi yìn ọ́ ní ìgbà méje lójúmọ́

165 Àlàáfíà púpọ̀ wà fún àwọn tí ó ní ìfẹ́ sí òfin rẹ,

166 Èmi yóò dúró de ìgbàlà rẹ, Olúwa,

167 Èmi gba òfin rẹ gbọ́,

168 Èmi ṣe ìgbọ́ràn sí ẹ̀kọ́ rẹ àti òfin rẹ,

169 Jẹ́ kí igbe mi wá sí iwájú rẹ, Olúwa;

170 Jẹ́ kí ẹ̀bẹ̀ mi wá sí iwájú rẹ;

171 Ètè mi yóò sọ ìyìn jáde,

172 Jẹ́ kí ahọ́n mi kọ orin ọ̀rọ̀ rẹ,

173 Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ ṣetán láti ràn mí lọ́wọ́,

174 Èmi wo ọ̀nà fún ìgbàlà rẹ, Olúwa,

175 Jẹ́ kí èmi wà láààyè ki èmi lè yìn ọ́,

176 Èmí ti ṣìnà bí àgùntàn tí ó sọnù.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado