Salmos 118

YOR

1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;

2 Jẹ́ kí Israẹli wí pé:

3 Jẹ́ kí ilé Aaroni wí pé:

4 Jẹ́ kí àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa wí pé:

5 Nínú ìrora mi, mo sọkún sí Olúwa,

6 Olúwa ń bẹ fún èmi; èmi kì yóò bẹ̀rù.

7 Olúwa ń bẹ fún mi; òun ni olùrànlọ́wọ́ mi.

8 Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa

9 Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa

10 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yí mi káàkiri,

11 Wọ́n yí mi káàkiri ní gbogbo ẹ̀gbẹ́,

12 Wọ́n gbá yìn ìn yí mi ká bí oyin,

13 Ìwọ tì mí gidigidi kí n lè ṣubú,

14 Olúwa ni agbára àti orin mi;

15 Ohùn ayọ̀ àti ìgbàlà ń bẹ nínú àgọ́ àwọn olódodo:

16 Ọwọ́ ọ̀tún Olúwa ní a gbéga;

17 Èmi kì yóò kú, ṣùgbọ́n èmi yóò yè,

18 Olúwa bá mi wí gidigidi,

19 Ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òdodo fún mi:

20 Èyí ni ìlẹ̀kùn Olúwa

21 Èmi yóò fi ọpẹ́ fún ọ, nítorí ó dá mi lóhùn;

22 Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀sílẹ̀,

23 Olúwa ti ṣe èyí,

24 Èyí ni ọjọ́ tí Olúwa dá:

25 Olúwa, gbà wá;

26 Ìbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa.

27 Olúwa ni Ọlọ́run,

28 Ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún ọ;

29 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado