Salmos 115

YOR

1 Kì í ṣe fún wa, Olúwa kì í ṣe fún wa,

2 Torí kí ni àwọn kèfèrí yóò ṣe sọ pé,

3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa wà lọ́run:

4 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,

5 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀,

6 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀:

7 Wọ́n ní ọwọ́, ṣùgbọ́n wọn kò lò ó,

8 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn;

9 Ìwọ Israẹli gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:

10 Ẹ̀ yin ilé Aaroni, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:

11 Ẹ̀ yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:

12 Olúwa tí ń ṣe ìrántí wa; yóò bùkún ilé Israẹli;

13 Ìbùkún ni fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa,

14 Olúwa yóò mú ọ pọ̀ sí i síwájú àti síwájú,

15 Ẹ fi ìbùkún fún Olúwa

16 Ọ̀run àní ọ̀run ni ti Olúwa:

17 Òkú kò lè yìn Olúwa,

18 Ṣùgbọ́n àwa ó fi ìbùkún fún Olúwa

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado