1 Kì í ṣe fún wa, Olúwa kì í ṣe fún wa,
2 Torí kí ni àwọn kèfèrí yóò ṣe sọ pé,
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa wà lọ́run:
4 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà,
5 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀,
6 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀:
7 Wọ́n ní ọwọ́, ṣùgbọ́n wọn kò lò ó,
8 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn;
9 Ìwọ Israẹli gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:
10 Ẹ̀ yin ilé Aaroni, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:
11 Ẹ̀ yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa:
12 Olúwa tí ń ṣe ìrántí wa; yóò bùkún ilé Israẹli;
13 Ìbùkún ni fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa,
14 Olúwa yóò mú ọ pọ̀ sí i síwájú àti síwájú,
15 Ẹ fi ìbùkún fún Olúwa
16 Ọ̀run àní ọ̀run ni ti Olúwa:
17 Òkú kò lè yìn Olúwa,
18 Ṣùgbọ́n àwa ó fi ìbùkún fún Olúwa