Provérbios 31

YOR

1 Àwọn ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ ti Lemueli ọba, ọ̀rọ̀ ẹ̀kọ́ tí ìyá rẹ̀ kọ́ ọ,

2 “Gbọ́ ìwọ ọmọ mi, gbọ́ ìwọ ọmọ inú mi!

3 Má ṣe lo agbára rẹ lórí obìnrin,

4 “Kì í ṣe fún àwọn ọba, ìwọ Lemueli,

5 kí wọn má ba à mu ọtí yó kí wọn sì gbàgbé ohun tí òfin wí,

6 Fi ọtí líle fún àwọn tí ń ṣègbé

7 Jẹ́ kí wọn mu ọtí kí wọn sì gbàgbé òsì wọn

8 “Sọ̀rọ̀ lórúkọ àwọn tí kò le sọ̀rọ̀ fúnra wọn

9 Sọ̀rọ̀ kí o sì ṣe ìdájọ́ àìṣègbè

10 Ta ni ó le rí aya oníwà rere?

11 Ọkọ rẹ̀ ní ìgbẹ́kẹ̀lé púpọ̀ nínú rẹ̀

12 Ire ní ó ń ṣe fún un, kì í ṣe ibi

13 Ó sa aṣọ irun àgùntàn olówùú àti ọ̀gbọ̀

14 Ó dàbí ọkọ̀ ojú omi tí àwọn oníṣòwò;

15 Ó dìde nígbà tí òkùnkùn sì kùn;

16 Ó kíyèsi oko kan, ó sì rà á;

17 Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ tagbára tagbára

18 Ó rí i pé òwò òun pé

19 Ní ọwọ́ rẹ̀, ó di kẹ̀kẹ́ òwú mú

20 O la ọwọ́ rẹ̀ sí àwọn tálákà

21 Nígbà tí òjò-dídì rọ̀, kò bẹ̀rù nítorí ìdílé rẹ̀

22 Ó ṣe aṣọ títẹ́ fún ibùsùn rẹ̀;

23 A bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀ ní ẹnu ibodè ìlú

24 Ó ń ṣe àwọn aṣọ dáradára ó sì ń tà wọ́n

25 Agbára àti ọlá ni ó wò ọ́ láṣọ

26 A sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọgbọ́n

27 Ó ń bojútó gbogbo ètò ilé rẹ̀

28 Àwọn ọmọ rẹ̀ dìde wọ́n sì pè é ní alábùkún

29 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ obìnrin ní ń ṣe nǹkan ọlọ́lá

30 Ojú dáradára a máa tan ni, ẹwà sì jẹ́ asán

31 Sì fún un ní èrè tí ó tọ́ sí i

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado