Provérbios 25

YOR

1 Wọ̀nyí ni àwọn òwe mìíràn tí Solomoni pa, tí àwọn ọkùnrin Hesekiah ọba Juda dà kọ.

2 Ògo Ọlọ́run ní láti fi ọ̀rọ̀ kan pamọ́;

3 Bí ọ̀run ṣe ga tó tí ayé sì jì

4 Mú ìdàrọ́ kúrò lára fàdákà

5 Mú ènìyàn búburú kúrò níwájú ọba

6 Má ṣe gbé ara rẹ ga níwájú ọba,

7 ó sàn kí ó wí fún ọ pé, “Gòkè wá síyìn-ín,”

8 Ohun tí o ti fi ojú ara rẹ rí

9 Bí o bá ń ṣe àwíjàre rẹ níwájú aládùúgbò rẹ,

10 àìṣe bẹ́ẹ̀ ẹni tí ó gbọ́ ọ le dójútì ọ́

11 Ọ̀rọ̀ tí a sọ ní àkókò tí ó yẹ

12 Bí i yẹtí wúrà tàbí ohun ọ̀ṣọ́ ti wúrà dáradára

13 Bí títutù òjò yìnyín ní àsìkò ìkórè

14 Bí ojú ṣíṣú àti afẹ́fẹ́ láìsí òjò

15 Nípa sùúrù a lè yí ọba lọ́kàn padà

16 Bí ìwọ bá rí oyin, jẹ ẹ́ ní ìwọ̀nba

17 Má ṣe máa lọ sí ilé aládùúgbò rẹ nígbà gbogbo

18 Bí ọ̀pá, idà tàbí ọ̀kọ̀ tí ó mú

19 Bí eyín tí ó bàjẹ́ tàbí ẹsẹ̀ tí ó rọ

20 Bí ẹni tí ó bọ́ra kalẹ̀ ní ọjọ́ tí òtútù mú,

21 Bí ebi bá ń pa ọ̀tá rẹ, fún un ní oúnjẹ jẹ;

22 Nípa ṣíṣe báyìí, ìwọ yóò wa ẹ̀yín iná lé e lórí

23 Bí afẹ́fẹ́ gúúsù ti í mú òjò wá,

24 Ó sàn láti gbé ní ibi igun kan lórí òrùlé

25 Bí omi tútù sí ọkàn tí ń ṣe àárẹ̀

26 Bí ìsun tí ó di àbàtà tàbí kànga tí omi rẹ̀ bàjẹ́

27 Kò dára láti jẹ oyin àjẹjù,

28 Bí ìlú tí odi rẹ̀ ti wó lulẹ̀

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado