1 Ti ènìyàn ni ìgbèrò inú ọkàn
2 Gbogbo ọ̀nà ènìyàn ni ó dàbí i pé ó dára lójú ara rẹ̀
3 Fi ohun gbogbo tí o bá ṣe lé Olúwa lọ́wọ́,
4 Olúwa ti ṣe ohun gbogbo láti mú kí ó rí bí ó ṣe fẹ́
5 Olúwa kórìíra gbogbo ẹni tí ń gbéraga lọ́kàn rẹ̀
6 Nípasẹ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́ a ṣe ètùtù ẹ̀ṣẹ̀
7 Nígbà tí ọ̀nà ènìyàn bá tẹ́ Olúwa lọ́rùn,
8 Ó sàn kí ó kéré pẹ̀lú òdodo
9 Ènìyàn a máa pète ọ̀nà ara rẹ̀ lọ́kàn an rẹ̀
10 Ètè ọba a máa sọ̀rọ̀ nípa àṣẹ sí i
11 Òdínwọ̀n àti òsùwọ̀n òtítọ́ wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa;
12 Àwọn ọba kórìíra ìwà àìtọ́
13 Àwọn ọba ní inú dídùn sí ètè tí ń ṣọ òtítọ́,
14 Ìránṣẹ́ ikú ni ìbínú ọba jẹ́
15 Nígbà tí ojú ọba bá túká, ó túmọ̀ sí ìyè;
16 Ó ti dára tó láti ní ọgbọ́n ju wúrà lọ
17 Òpópó ọ̀nà àwọn ẹni dídúró ṣinṣin yàgò fún ibi,
18 Ìgbéraga ní í ṣáájú ìparun,
19 Ó sàn láti jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ ọkàn láàrín àwọn olùpọ́njú
20 Ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé ẹ̀kọ́ yóò rí ìre,
21 Àwọn tí ó gbọ́n nínú ọkàn là ń pè ní olóye
22 Òye jẹ́ orísun ìyè fún àwọn tí ó ní i,
23 Ọkàn ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ṣọ́ ẹnu rẹ̀
24 Ọ̀rọ̀ ìtura dàbí afárá oyin
25 Ọ̀nà kan tí ó dàbí i pé ó dára lójú ènìyàn
26 Ọkàn alágbàṣe ń ṣiṣẹ́ fún ara rẹ̀;
27 Ènìyàn búburú ń pète
28 Aláyídáyidà ènìyàn dá ìjà sílẹ̀
29 Oníjàgídíjàgan ènìyàn tan aládùúgbò rẹ̀
30 Ẹni tí ń ṣẹ́jú ń pètekéte;
31 Adé ògo ni ewú orí jẹ́,
32 Ó sàn láti jẹ́ onísùúrù ju ajagun ènìyàn lọ,
33 A ṣẹ́ kèké si ìṣẹ́po aṣọ,