Provérbios 16

YOR

1 Ti ènìyàn ni ìgbèrò inú ọkàn

2 Gbogbo ọ̀nà ènìyàn ni ó dàbí i pé ó dára lójú ara rẹ̀

3 Fi ohun gbogbo tí o bá ṣe lé Olúwa lọ́wọ́,

4 Olúwa ti ṣe ohun gbogbo láti mú kí ó rí bí ó ṣe fẹ́

5 Olúwa kórìíra gbogbo ẹni tí ń gbéraga lọ́kàn rẹ̀

6 Nípasẹ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́ a ṣe ètùtù ẹ̀ṣẹ̀

7 Nígbà tí ọ̀nà ènìyàn bá tẹ́ Olúwa lọ́rùn,

8 Ó sàn kí ó kéré pẹ̀lú òdodo

9 Ènìyàn a máa pète ọ̀nà ara rẹ̀ lọ́kàn an rẹ̀

10 Ètè ọba a máa sọ̀rọ̀ nípa àṣẹ sí i

11 Òdínwọ̀n àti òsùwọ̀n òtítọ́ wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa;

12 Àwọn ọba kórìíra ìwà àìtọ́

13 Àwọn ọba ní inú dídùn sí ètè tí ń ṣọ òtítọ́,

14 Ìránṣẹ́ ikú ni ìbínú ọba jẹ́

15 Nígbà tí ojú ọba bá túká, ó túmọ̀ sí ìyè;

16 Ó ti dára tó láti ní ọgbọ́n ju wúrà lọ

17 Òpópó ọ̀nà àwọn ẹni dídúró ṣinṣin yàgò fún ibi,

18 Ìgbéraga ní í ṣáájú ìparun,

19 Ó sàn láti jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ ọkàn láàrín àwọn olùpọ́njú

20 Ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé ẹ̀kọ́ yóò rí ìre,

21 Àwọn tí ó gbọ́n nínú ọkàn là ń pè ní olóye

22 Òye jẹ́ orísun ìyè fún àwọn tí ó ní i,

23 Ọkàn ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ṣọ́ ẹnu rẹ̀

24 Ọ̀rọ̀ ìtura dàbí afárá oyin

25 Ọ̀nà kan tí ó dàbí i pé ó dára lójú ènìyàn

26 Ọkàn alágbàṣe ń ṣiṣẹ́ fún ara rẹ̀;

27 Ènìyàn búburú ń pète

28 Aláyídáyidà ènìyàn dá ìjà sílẹ̀

29 Oníjàgídíjàgan ènìyàn tan aládùúgbò rẹ̀

30 Ẹni tí ń ṣẹ́jú ń pètekéte;

31 Adé ògo ni ewú orí jẹ́,

32 Ó sàn láti jẹ́ onísùúrù ju ajagun ènìyàn lọ,

33 A ṣẹ́ kèké si ìṣẹ́po aṣọ,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado