1 “Ẹ̀yin ènìyàn Benjamini, sá sí ibi ààbò!
2 Èmi yóò pa ọmọbìnrin Sioni run,
3 Olùṣọ́-àgùntàn pẹ̀lú agbo wọn yóò gbóguntì wọ́n.
4 “Ẹ ya ará yín sí mímọ́ láti bá a jagun!
5 Nítorí náà, ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú ní àṣálẹ́
6 Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí:
7 Gẹ́gẹ́ bí kànga ṣe ń da omi inú rẹ̀ sílẹ̀,
8 Ìwọ Jerusalẹmu, gba ìkìlọ̀,
9 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:
10 Ta ni ẹni tí mo lè bá sọ̀rọ̀ àti tí mo lè fún ní ìmọ̀ràn?
11 Èmi kún fún ìbínú Olúwa,
12 Ilé wọn o sì di ti ẹlòmíràn,
13 “Láti orí ẹni tí ó kéré sí orí ẹni tí ó tóbi ju,
14 Wọ́n sì ń wo ọgbẹ́ àwọn ènìyàn
15 Ojú ha a tì wọ́n nítorí ìwà ìríra wọn bí?
16 Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
17 Èmi yan olùṣọ́ fún un yín,
18 Nítorí náà, gbọ́ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè;
19 Gbọ́, ìwọ ayé!
20 Èrè wo ni ó wà fún mi nínú tùràrí láti Ṣeba wá,
21 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí:
22 Báyìí ni Olúwa wí:
23 Wọ́n sì dìmọ́ra pẹ̀lú ọrun àti ọ̀kọ̀,
24 Àwa ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,
25 Má ṣe jáde lọ sí orí pápá
26 Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀,
27 “Èmi ti fi ẹ́ ṣe ẹni tí yóò máa yọ́
28 Ọlọ́tẹ̀ tí ọkàn rẹ̀ le ní gbogbo wọn.
29 Ewìrì a fẹ́ná kíkankíkan,
30 A pè wọ́n ní fàdákà tí a kọ̀sílẹ̀,