Jeremias 30

YOR

1 Ọ̀rọ̀ tí ó tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, wí pé:

2 “Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, pé: ‘Ìwọ kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti bá ọ sọ sínú ìwé kan.

3 Ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí ń ó mú àwọn ènìyàn mi, àwọn ọmọ Israẹli àti Juda kúrò nínú ìgbèkùn, tí n ó sì dá wọn padà sí orí ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn baba ńlá wọn láti ní,’ ni Olúwa Ọlọ́run wí.”

4 Ìwọ̀nyí ni àwọn ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run sí Israẹli àti Juda:

5 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

6 Béèrè kí o sì rí.

7 Ọjọ́ náà yóò ha ti burú tó!

8 “ ‘Ní ọjọ́ náà,’ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé,

9 Dípò bẹ́ẹ̀ wọn yóò máa sin Olúwa Ọlọ́run wọn

10 “ ‘Nítorí náà, má ṣe bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,

11 Èmi wà pẹ̀lú rẹ, n ó sì gbà ọ́,’

12 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

13 Kò sí ẹnìkan tí yóò bẹ̀bẹ̀ fún àìṣedéédéé yín,

14 Gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ ti gbàgbé rẹ,

15 Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń kígbe nítorí ọgbẹ́ yín,

16 “ ‘Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ṣe yín ní ibi ni ibi yóò bá,

17 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìlera fún yín,

18 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

19 Láti ẹnu wọn ni orin ọpẹ́ àti

20 Ọmọ ọmọ wọn yóò wà bí i ti ìgbàanì

21 Ọ̀kan nínú wọn ni yóò jẹ́ olórí wọn,

22 ‘Nítorí náà, ẹ̀yin yóò jẹ́ ènìyàn mi,

23 Wò ó, ìbínú Olúwa yóò tú jáde,

24 Ìbínú ńlá Olúwa kò ní dẹ̀yìn lẹ́yìn

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado