1 Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ fún yín ẹ̀yin ilé Israẹli.
2 Báyìí ni Olúwa wí:
3 Nítorí pé asán ni àṣà àwọn ènìyàn,
4 Wọ́n fi fàdákà àti wúrà ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́.
5 Wọ́n wé mọ́ igi bí ẹ̀gúnsí inú oko,
6 Kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ Olúwa;
7 Ta ni kò yẹ kí ó bẹ̀rù rẹ?
8 Gbogbo wọn jẹ́ aláìlóye àti aṣiwèrè,
9 Fàdákà tí a ti kàn ni a mú wá láti Tarṣiṣi,
10 Ṣùgbọ́n Olúwa ni Ọlọ́run tòótọ́,
11 “Sọ èyí fún wọn: ‘Àwọn ọlọ́run kéékèèké tí kò dá ọ̀run àti ayé ni yóò ṣègbé láti ayé àti ní abẹ́ ọ̀run.’ ”
12 Ọlọ́run dá ayé pẹ̀lú agbára rẹ̀,
13 Nígbà tí ó bá sán àrá, àwọn omi lọ́run a sì pariwo;
14 Gbogbo ènìyàn jẹ́ aṣiwèrè àti aláìnímọ̀,
15 Asán ni wọ́n, iṣẹ́ ìṣìnà;
16 Ẹni tí ó bá jẹ́ ìpín Jakọbu kò sì dàbí èyí,
17 Kó ẹrù rẹ kúrò láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀
18 Nítorí èyí ni Olúwa wí:
19 Ègbé ni fún mi nítorí ìpalára mi!
20 Àgọ́ mi bàjẹ́,
21 Àwọn olùṣọ́-àgùntàn jẹ́ aṣiwèrè,
22 Fetísílẹ̀! ariwo igbe ń bọ̀,
23 Èmi mọ̀ Olúwa wí pé ọ̀nà ènìyàn kì í ṣe ti ara rẹ̀,
24 Tún mi ṣe Olúwa, pẹ̀lú ìdájọ́ nìkan
25 Tú ìbínú rẹ jáde sórí àwọn orílẹ̀-èdè