Jeremias 10

YOR

1 Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ fún yín ẹ̀yin ilé Israẹli.

2 Báyìí ni Olúwa wí:

3 Nítorí pé asán ni àṣà àwọn ènìyàn,

4 Wọ́n fi fàdákà àti wúrà ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́.

5 Wọ́n wé mọ́ igi bí ẹ̀gúnsí inú oko,

6 Kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ Olúwa;

7 Ta ni kò yẹ kí ó bẹ̀rù rẹ?

8 Gbogbo wọn jẹ́ aláìlóye àti aṣiwèrè,

9 Fàdákà tí a ti kàn ni a mú wá láti Tarṣiṣi,

10 Ṣùgbọ́n Olúwa ni Ọlọ́run tòótọ́,

11 “Sọ èyí fún wọn: ‘Àwọn ọlọ́run kéékèèké tí kò dá ọ̀run àti ayé ni yóò ṣègbé láti ayé àti ní abẹ́ ọ̀run.’ ”

12 Ọlọ́run dá ayé pẹ̀lú agbára rẹ̀,

13 Nígbà tí ó bá sán àrá, àwọn omi lọ́run a sì pariwo;

14 Gbogbo ènìyàn jẹ́ aṣiwèrè àti aláìnímọ̀,

15 Asán ni wọ́n, iṣẹ́ ìṣìnà;

16 Ẹni tí ó bá jẹ́ ìpín Jakọbu kò sì dàbí èyí,

17 Kó ẹrù rẹ kúrò láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀

18 Nítorí èyí ni Olúwa wí:

19 Ègbé ni fún mi nítorí ìpalára mi!

20 Àgọ́ mi bàjẹ́,

21 Àwọn olùṣọ́-àgùntàn jẹ́ aṣiwèrè,

22 Fetísílẹ̀! ariwo igbe ń bọ̀,

23 Èmi mọ̀ Olúwa wí pé ọ̀nà ènìyàn kì í ṣe ti ara rẹ̀,

24 Tún mi ṣe Olúwa, pẹ̀lú ìdájọ́ nìkan

25 Tú ìbínú rẹ jáde sórí àwọn orílẹ̀-èdè

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado