1 Elihu sì wí pe:
2 “Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé,
3 Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ,
4 “Èmi ó dá ọ lóhùn
5 Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì
6 Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí?
7 Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un,
8 Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ;
9 “Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe;
10 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé,
11 tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ,
12 Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn
13 Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán;
14 Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i,
15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni,
16 Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀