Jó 35

YOR

1 Elihu sì wí pe:

2 “Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé,

3 Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ,

4 “Èmi ó dá ọ lóhùn

5 Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì

6 Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí?

7 Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un,

8 Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ;

9 “Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe;

10 Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé,

11 tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ,

12 Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn

13 Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán;

14 Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i,

15 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni,

16 Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado