Jó 25

YOR

1 Nígbà náà ní Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn wí pé,

2 “Ìjọba àti ẹ̀rù ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,

3 Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ní ìyè bí,

4 Èéha ti ṣe tí a ó fi dá ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?

5 Kíyèsi i, òṣùpá kò sì lè tàn ìmọ́lẹ̀,

6 kí a má sọ ènìyàn tí i ṣe ìdin,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado