Jó 23

YOR

1 Ìgbà náà ni Jobu sì dáhùn wí pé,

2 “Àní lónìí ni ọ̀ràn mi korò;

3 Háà! èmi ìbá mọ ibi tí èmí ìbá wá

4 Èmi ìbá sì to ọ̀ràn náà níwájú rẹ̀,

5 Èmi ìbá sì mọ ọ̀rọ̀ tí òun ìbá fi dá mi lóhùn;

6 Yóò ha fi agbára ńlá bá mi wíjọ́ bí?

7 Níbẹ̀ ni olódodo le è bá a wíjọ́,

8 “Sì wò ó, bí èmi bá lọ sí iwájú,

9 Ni apá òsì bí ó bá ṣiṣẹ́ níbẹ̀, èmi kò rí i,

10 Ṣùgbọ́n òun mọ ọ̀nà tí èmi ń tọ̀,

11 Ẹsẹ̀ mí ti tẹ̀lé ipasẹ̀ ìrìn rẹ̀;

12 Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò padà sẹ́yìn kúrò nínú òfin ẹnu rẹ̀,

13 “Ṣùgbọ́n onínú kan ni òun, ta ni yóò sì yí i padà?

14 Nítòótọ́ ohun tí a ti yàn fún mi ní í ṣe;

15 Nítorí náà ni ara kò ṣe rọ̀ mí níwájú rẹ̀;

16 Nítorí pé Ọlọ́run ti pá mi ní àyà,

17 Nítorí tí a kò tí ì ké mi kúrò níwájú òkùnkùn,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado