Jó 18

YOR

1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn, ó sì wí pé,

2 “Nígbà wo ni ẹ̀yin yóò tó fi ìdí ọ̀rọ̀ tì;

3 Nítorí kí ni a ṣe ń kà wá sí bí ẹranko,

4 Ìwọ fa ara rẹ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ nínú ìbínú rẹ̀;

5 “Nítòótọ́ ìmọ́lẹ̀ ènìyàn búburú ni a ó pa kúrò,

6 Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn nínú àgọ́ rẹ̀,

7 Ìrìn ẹsẹ̀ agbára rẹ̀ yóò di fífọ;

8 Nípa ẹ̀ṣẹ̀ òun tìkára rẹ̀ ó ti bọ́ sínú àwọ̀n,

9 Tàkúté ni yóò mú un ní gìgísẹ̀,

10 A dẹkùn sílẹ̀ fún un lórí ilẹ̀,

11 Ẹ̀rù ńlá yóò bà á ní ìhà gbogbo,

12 Àìlera rẹ̀ yóò di púpọ̀ fún ebi,

13 Yóò jẹ ẹ̀yà ara rẹ̀;

14 A ó fà á tu kúrò nínú àgọ́ tí ó gbẹ́kẹ̀lé,

15 Yóò sì máa jókòó nínú àgọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe tirẹ̀;

16 Gbòǹgbò rẹ̀ yóò gbẹ níṣàlẹ̀,

17 Ìrántí rẹ̀ yóò parun kúrò ni ayé,

18 A ó sì lé e láti inú ìmọ́lẹ̀ sí inú òkùnkùn,

19 Kì yóò ní ọmọ tàbí ọmọ ọmọ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀,

20 Ẹnu yóò ya àwọn ìran ti ìwọ̀-oòrùn sí ìgbà ọjọ́ rẹ̀,

21 Nítòótọ́ irú bẹ́ẹ̀ ni ibùgbé àwọn

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado