1 Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn, ó sì wí pé,
2 “Nígbà wo ni ẹ̀yin yóò tó fi ìdí ọ̀rọ̀ tì;
3 Nítorí kí ni a ṣe ń kà wá sí bí ẹranko,
4 Ìwọ fa ara rẹ ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ nínú ìbínú rẹ̀;
5 “Nítòótọ́ ìmọ́lẹ̀ ènìyàn búburú ni a ó pa kúrò,
6 Ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn nínú àgọ́ rẹ̀,
7 Ìrìn ẹsẹ̀ agbára rẹ̀ yóò di fífọ;
8 Nípa ẹ̀ṣẹ̀ òun tìkára rẹ̀ ó ti bọ́ sínú àwọ̀n,
9 Tàkúté ni yóò mú un ní gìgísẹ̀,
10 A dẹkùn sílẹ̀ fún un lórí ilẹ̀,
11 Ẹ̀rù ńlá yóò bà á ní ìhà gbogbo,
12 Àìlera rẹ̀ yóò di púpọ̀ fún ebi,
13 Yóò jẹ ẹ̀yà ara rẹ̀;
14 A ó fà á tu kúrò nínú àgọ́ tí ó gbẹ́kẹ̀lé,
15 Yóò sì máa jókòó nínú àgọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe tirẹ̀;
16 Gbòǹgbò rẹ̀ yóò gbẹ níṣàlẹ̀,
17 Ìrántí rẹ̀ yóò parun kúrò ni ayé,
18 A ó sì lé e láti inú ìmọ́lẹ̀ sí inú òkùnkùn,
19 Kì yóò ní ọmọ tàbí ọmọ ọmọ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀,
20 Ẹnu yóò ya àwọn ìran ti ìwọ̀-oòrùn sí ìgbà ọjọ́ rẹ̀,
21 Nítòótọ́ irú bẹ́ẹ̀ ni ibùgbé àwọn