1 “Ènìyàn tí a bí nínú obìnrin,
2 Ó jáde wá bí ìtànná ewéko, a sì ké e lulẹ̀;
3 Ìwọ sì ń síjú rẹ wò irú èyí ni?
4 Ta ni ó lè mú ohun mímọ́ láti inú àìmọ́ jáde wá?
5 Ǹjẹ́ a ti pinnu ọjọ́ rẹ̀,
6 Yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, kí ó lè sinmi,
7 “Nítorí pé ìrètí wà fún igi, bí a bá
8 Bí gbòǹgbò rẹ̀ tilẹ̀ di ogbó nínú ilẹ̀,
9 síbẹ̀ nígbà tí ó bá gbóòórùn omi,
10 Ṣùgbọ́n ènìyàn kú, a sì dàánù,
11 “Bí omi ti í tán nínú ipa odò,
12 bẹ́ẹ̀ ni ènìyàn dùbúlẹ̀ tí kò sì dìde mọ́;
13 “Háà! ìwọ ìbá fi mí pamọ́ ní ipò òkú,
14 Bí ènìyàn bá kú yóò sì tún yè bí?
15 Ìwọ ìbá pè, èmi ìbá sì dá ọ lóhùn;
16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ń kaye ìṣísẹ̀ mi;
17 A fi èdìdì di ìrékọjá mi sínú àpò,
18 “Àti nítòótọ́ òkè ńlá tí ó ṣubú, ó dasán,
19 Omi a máa yinrin òkúta, ìwọ a sì
20 Ìwọ ṣẹ́gun rẹ̀ láéláé, òun sì kọjá lọ!
21 Àwọn ọmọ rẹ̀ bọ́ sí ipò ọlá, òun kò sì mọ̀;
22 Ṣùgbọ́n ẹran-ara rẹ̀ ni yóò rí ìrora