Isaías 40

YOR

1 Ẹ tù ú nínú, ẹ tu ènìyàn mi nínú,

2 Sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ fún Jerusalẹmu

3 Ohùn ẹni tí ń kígbe ní ijù:

4 Gbogbo àfonífojì ni a ó gbé sókè,

5 Ògo Olúwa yóò sì di mí mọ̀,

6 Ohùn kan wí pé, “Kígbe sókè.”

7 Koríko ń rọ ìtànná sì ń rẹ̀,

8 Koríko ń rọ ìtànná sì ń rẹ̀,

9 Ìwọ tí o mú ìyìn ayọ̀ wá sí Sioni,

10 Wò ó, Olúwa Olódùmarè náà ń bọ̀ wá pẹ̀lú agbára,

11 Ó ń tọ́ àwọn agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn:

12 Ta ni ó tiwọn omi nínú kòtò ọwọ́ rẹ̀,

13 Ta ni ó ti mọ ọkàn Olúwa,

14 Ta ni Olúwa ké sí kí ó là á lọ́yẹ

15 Nítòótọ́ àwọn orílẹ̀-èdè dàbí i ẹ̀kún omi nínú garawa;

16 Lebanoni kò tó fún pẹpẹ iná,

17 Níwájú rẹ̀ ni gbogbo orílẹ̀-èdè dàbí ohun tí kò sí;

18 Ta ni nígbà náà tí ìwọ yóò fi Ọlọ́run wé?

19 Ní ti ère, oníṣọ̀nà ni ó dà á,

20 Ọkùnrin kan tí ó tálákà jù kí ó lè mú

21 Ǹjẹ́ o kò tí ì mọ̀

22 Òun jókòó lórí ìtẹ́ ní òkè òbírí ilẹ̀ ayé,

23 Ó sọ àwọn ọmọ ọba di asán

24 Gẹ́rẹ́ tí a ti gbìn wọ́n,

25 “Ta ni ẹ ó fi mi wé?

26 Gbé ojú rẹ sókè kí o sì wo àwọn ọ̀run.

27 Èéṣe tí o fi sọ, ìwọ Jakọbu?

28 Ìwọ kò tí ì mọ̀?

29 Ó ń fi agbára fún àwọn aláàárẹ̀

30 Àní, ó ń rẹ̀ wọ́n àwọn ọ̀dọ́, wọ́n ń rẹ̀wẹ̀sì,

31 ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado