1 Ẹ tù ú nínú, ẹ tu ènìyàn mi nínú,
2 Sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ fún Jerusalẹmu
3 Ohùn ẹni tí ń kígbe ní ijù:
4 Gbogbo àfonífojì ni a ó gbé sókè,
5 Ògo Olúwa yóò sì di mí mọ̀,
6 Ohùn kan wí pé, “Kígbe sókè.”
7 Koríko ń rọ ìtànná sì ń rẹ̀,
8 Koríko ń rọ ìtànná sì ń rẹ̀,
9 Ìwọ tí o mú ìyìn ayọ̀ wá sí Sioni,
10 Wò ó, Olúwa Olódùmarè náà ń bọ̀ wá pẹ̀lú agbára,
11 Ó ń tọ́ àwọn agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn:
12 Ta ni ó tiwọn omi nínú kòtò ọwọ́ rẹ̀,
13 Ta ni ó ti mọ ọkàn Olúwa,
14 Ta ni Olúwa ké sí kí ó là á lọ́yẹ
15 Nítòótọ́ àwọn orílẹ̀-èdè dàbí i ẹ̀kún omi nínú garawa;
16 Lebanoni kò tó fún pẹpẹ iná,
17 Níwájú rẹ̀ ni gbogbo orílẹ̀-èdè dàbí ohun tí kò sí;
18 Ta ni nígbà náà tí ìwọ yóò fi Ọlọ́run wé?
19 Ní ti ère, oníṣọ̀nà ni ó dà á,
20 Ọkùnrin kan tí ó tálákà jù kí ó lè mú
21 Ǹjẹ́ o kò tí ì mọ̀
22 Òun jókòó lórí ìtẹ́ ní òkè òbírí ilẹ̀ ayé,
23 Ó sọ àwọn ọmọ ọba di asán
24 Gẹ́rẹ́ tí a ti gbìn wọ́n,
25 “Ta ni ẹ ó fi mi wé?
26 Gbé ojú rẹ sókè kí o sì wo àwọn ọ̀run.
27 Èéṣe tí o fi sọ, ìwọ Jakọbu?
28 Ìwọ kò tí ì mọ̀?
29 Ó ń fi agbára fún àwọn aláàárẹ̀
30 Àní, ó ń rẹ̀ wọ́n àwọn ọ̀dọ́, wọ́n ń rẹ̀wẹ̀sì,
31 ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa