1 Ègbé ni fún àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sí
2 Síbẹ̀síbẹ̀ òun pẹ̀lú jẹ́ ọlọ́gbọ́n ó sì lè mú ìparun wá;
3 Ṣùgbọ́n ènìyàn lásán ni àwọn ará Ejibiti
4 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi:
5 Gẹ́gẹ́ bí àwọn ẹyẹ ti ń rábàbà lókè
6 Ẹ padà sọ́dọ̀ ẹni tí ẹ ti ṣọ̀tẹ̀ sí gidigidi, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
7 Nítorí ní ọjọ́ náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóò kọ àwọn ère fàdákà àti wúrà tí ọwọ́ ẹ̀ṣẹ̀ yín ti ṣe.
8 “Asiria yóò ṣubú lọ́wọ́ idà kan tí kò ti ọwọ́ ènìyàn wá;
9 Àpáta rẹ yóò kọjá lọ fún ẹ̀rù;