1 Kíyèsi i, Olúwa yóò sọ ohun
2 bákan náà ni yóò sì rí
3 Ilé ayé ni a ó sọ di ahoro pátápátá
4 Ilẹ̀ ayé ti gbẹ ó sì sá,
5 àwọn ènìyàn ayé ti bà á jẹ́;
6 Nítorí náà, ègún kan ti jẹ ayé run;
7 Wáìnì tuntun ti gbẹ, àjàrà sì ti rọ,
8 Àríyá ti ṣaworo ti dákẹ́
9 Kò ṣe é ṣe fún wọn láti máa mu wáìnì pẹ̀lú orin kíkọ mọ́
10 Ìlú tí a run ti dahoro,
11 Ní òpópónà ni wọ́n ti ń kígbe fún wáìnì
12 Ìlú ni a ti fi sílẹ̀ ní ahoro,
13 Bẹ́ẹ̀ ni yóò sì rí ní orí ilẹ̀ ayé
14 Wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sì hó fún ayọ̀;
15 Nítorí náà ní ìlà-oòrùn ẹ fi ògo fún Olúwa;
16 Láti òpin ayé wá ni a ti gbọ́ orin;
17 Ìpayà, isà òkú, àti ìdẹ̀kùn ń dúró dè ọ́,
18 Ẹnikẹ́ni tí ó bá sá nítorí ariwo ìpayà
19 Ilẹ̀ ayé ti fọ́
20 Ilẹ̀ ayé yí gbiri bí ọ̀mùtí,
21 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa yóò jẹ ẹ́ ní yà
22 A ó sì kó wọn jọ pọ̀,
23 A ó rẹ òṣùpá sílẹ̀, ojú yóò sì ti oòrùn;