1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun.
2 Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí
3 Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí,
4 Ọkàn mí dàrú,
5 Wọ́n tẹ́ tábìlì,
6 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi:
7 Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun
8 Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan,
9 Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun
10 Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà,
11 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi.
12 Alóre náà dáhùn wí pé,
13 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia.
14 gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ;
15 Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà,
16 Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
17 Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.